I am an independent Yorùbá Language Specialist, Culture Enthusiast, Translator, Tutor and a Visual Storyteller.
I hold a Bachelor Degree in Yoruba and Communication Arts from the prestigious Lagos State University, Nigeria and a Masters degree (in view) in Yorùbá Literature and Culture.
You can follow me on social media platforms
Facebook: facebook.com/iyayooba
Twitter: Twitter.com/iyayoruba
Instagram: instagram.com/iya_yoruba
Àṣẹ̀sẹ̀tẹ̀jáde ìròyìn látọwọ́ọ Iya Yoruba
Fún ìgbà àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdèe Brazil, ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin di ọmọ ìgbìmọ̀ ìjọba
Joenia ni ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin àkọ́kọ́ tí ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin ní Brazil, òun sì ni agbẹjọ́rò tí ó jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ àkọ́kọ́ tí yóò gbejọ́rò ní Ilé-ẹjọ́ Gíga jùlọ.
Twitter @DigiAfricanLang 2019

Tweets by @DigiAfricanLang Bẹ̀rẹ̀ láti ogúnjọ́ oṣù Ẹrẹ́nà títí di òpin ọdún-un 2019, àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀ ní orí ẹ̀rọ ayárabíàṣá á máa ṣe ‘ọ̀ọ̀wẹ̀’ láti ṣàkóso aṣàmúlò Túwítà @DigiAfricanLang ní...
#FreeAmade: Akọ̀ròyìn tí a mú tí a sì dá lóró lẹ́yìn tí ó kọ ìròyìn lórí ìwà jàgídí jàgan tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní Àríwá Mozambique

Àwọn ọlọ́pàá Mozambique ju akọ̀ròyìn náà sí àhámọ̀ níbi tí ó ti ń jábọ̀ ìròyìn ní Cabo Delgado
Ilé-iṣẹ́ Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìbílẹ̀ Fagilé Ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn ajìjàǹgbara LGBT lẹ́yìn ìhalẹ̀mọ́ sí olóòtú

Èébú ìkórìíra-ìbálòpọ̀-láàárín-akọ-àti-akọ ní orí ayélujára kò ṣí ọkàn-an olóòtú kúrò, àmọ́ ìpè ẹni àjèjì ń dá ẹ̀ru ìwà ìkà bá àwọn àlejòo rẹ̀.