I am an independent Yorùbá Language Specialist, Culture Enthusiast, Translator, Tutor and a Visual Storyteller.
I hold a Bachelor Degree in Yoruba and Communication Arts from the prestigious Lagos State University, Nigeria and a Masters degree (in view) in Yorùbá Literature and Culture.
You can follow me on social media platforms
Facebook: facebook.com/iyayooba
Twitter: Twitter.com/iyayoruba
Instagram: instagram.com/iya_yoruba
Àṣẹ̀sẹ̀tẹ̀jáde ìròyìn látọwọ́ọ Iya Yoruba
Orílẹ̀-Èdè Nàìjíríà fi òfin de ìrìn-àjò lójúnà ìṣàmójútó àwọn tó ti kó kòkòrò àìfojúrí COVID 19
Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lórí ayélujára béèrè fún ìfòfindè arìnrìnàjò láti orílẹ̀-èdè tí COVID-19 ti gbilẹ̀. Èyí á ró ojúṣẹ́ orílẹ̀-èdè sí ìtànkálẹ̀ yìí lágbára.
Twitter di pápá ìròyìn ayédèrú lásìkò Ìdìbò ọdún-un 2019 ní Nàìjíríà
Twitter di pápá ayédèrú ìròyìn ìtako ẹ̀yà kan àti ìsọkiri ṣáájú ìdìbò, lásìkò ìdìbò àti lẹ́yìn ìdìbò ti ọdún-un 2019 lórílẹ̀-èdèe Nàìjíríà
Wọ́n fagi lé ìfìwépè Adarí iléeṣẹ́ tó ń ṣètò Ìṣàjò-papọ̀-wa-ọkọ̀-kí-n-wa-ọkọ̀ sí iléeṣẹ́ tẹlifíṣàn Russia lẹ́yìn tí olóòtú ètò rí i pé obìnrin ni
Russia ṣì ní iṣẹ́ tó pọ̀ láti ṣe lórí ọ̀rọ̀ ìbádọ́gba akọ àti abo.
Burundi: Kọ Ìkọkúkọ sórí àwòrán Ààrẹ — kí o wẹ̀wọ̀n
"Bí mo bá ṣe èyí ní Burundi ti Nkurunziza, Mo lè wẹ̀wọ̀n."
Fún ìgbà àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdèe Brazil, ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin di ọmọ ìgbìmọ̀ ìjọba
Joenia ni ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin àkọ́kọ́ tí ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin ní Brazil, òun sì ni agbẹjọ́rò tí ó jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ àkọ́kọ́ tí yóò gbejọ́rò ní Ilé-ẹjọ́ Gíga jùlọ.
Twitter @DigiAfricanLang 2019
Tweets by @DigiAfricanLang Bẹ̀rẹ̀ láti ogúnjọ́ oṣù Ẹrẹ́nà títí di òpin ọdún-un 2019, àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀ ní orí ẹ̀rọ ayárabíàṣá á máa ṣe ‘ọ̀ọ̀wẹ̀’ láti ṣàkóso aṣàmúlò Túwítà @DigiAfricanLang ní tẹ̀lé-ǹ-tẹ̀lé, aṣàmúlò tuntun náà á máa ṣàfihàn ipa tí ìmọ̀-ẹ̀rọ ń kó nínú ìgbélárugẹ àti ìgbéǹde àwọn èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀....
#FreeAmade: Akọ̀ròyìn tí a mú tí a sì dá lóró lẹ́yìn tí ó kọ ìròyìn lórí ìwà jàgídí jàgan tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní Àríwá Mozambique
Àwọn ọlọ́pàá Mozambique ju akọ̀ròyìn náà sí àhámọ̀ níbi tí ó ti ń jábọ̀ ìròyìn ní Cabo Delgado
Ilé-iṣẹ́ Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìbílẹ̀ Fagilé Ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn ajìjàǹgbara LGBT lẹ́yìn ìhalẹ̀mọ́ sí olóòtú
Èébú ìkórìíra-ìbálòpọ̀-láàárín-akọ-àti-akọ ní orí ayélujára kò ṣí ọkàn-an olóòtú kúrò, àmọ́ ìpè ẹni àjèjì ń dá ẹ̀ru ìwà ìkà bá àwọn àlejòo rẹ̀.