Ìròyìn asọ̀tàn nípa Ìbò
Ìròyìn nípa Ìbò
Ẹ̀rọ Alátagbà ni a fi gbé àwọn ìròyìn irọ́ àti ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹyà jáde lásìkò ìdìbò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà
Ìbò ọdún-un 2019 orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà rí àwọn ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin láìròtẹ́lẹ̀ nípasẹ̀ẹ ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ àti ọ̀nà ìtànkálẹ̀ ìròyìn lórí ayélujára, pabambarì lóríi gbàgede Twitter.
Àwọn ọ̀gágun ajagun fẹ̀yìntì orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wọ̀yáàjà láti nípa lórí ètò ìdìbò ọdún-un 2019
Olusegun Obasanjo, former military head of state and later Nigeria’s democratically elected president, has consistently criticized successive governments in Nigeria.
Mọ àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ọdún 2019
Ìdíje fún Àpáta Agbára ti ń lọ — àga Ààrẹ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà. Mọ àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ọdún-un 2019.