Ìròyìn nípa Ìbò
Fún ìgbà àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdèe Brazil, ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin di ọmọ ìgbìmọ̀ ìjọba
Joenia ni ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin àkọ́kọ́ tí ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin ní Brazil, òun sì ni agbẹjọ́rò tí ó jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ àkọ́kọ́ tí yóò gbejọ́rò ní Ilé-ẹjọ́ Gíga jùlọ.
Pẹ̀lú àìbalẹ̀-ọkàn tí ó ń pọ̀ sí i ní ìmúra ìbò ààrẹ ọdún-un 2019, Ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń bẹ̀rùu pípa ẹ̀rọ-ayélujára

Lílo ẹ̀rọ-alátagbà fún pípe àkíyèsí sí ìrúfin ìjọba àti ìwà tí kò bá òfin mu ti fa ìbẹ̀rù wípé ìtẹríbọlẹ̀ ní orí ayélujára ní àsìkò ìbò tí ó ń bọ̀.
Àwọn ọ̀gágun ajagun fẹ̀yìntì orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wọ̀yáàjà láti nípa lórí ètò ìdìbò ọdún-un 2019
Olusegun Obasanjo, former military head of state and later Nigeria’s democratically elected president, has consistently criticized successive governments in Nigeria.
Mọ àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ọdún 2019
Ìdíje fún Àpáta Agbára ti ń lọ — àga Ààrẹ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà. Mọ àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ọdún-un 2019.