BABATÚNDÉ ỌLÁṢAYỌ̀ PÓPÓỌLÁ holds a Bachelor of Degree in view in Linguistics/Yoruba from University of Lagos. His final year thesis is on “The used of Oral Literature in Afọ̀njá movie” Supervisor: Caleb S. Ọ̀wọ́adé M.A. (LAGOS)
He is currently a Research Assistant to Prof. Ọlàdiípọ̀ Ajíbóyè of the Department of Linguistics African and Asian Studies, Unilag and Dr. Abísóyè Ẹlẹ́shin of Institute of African and Diaspora Studies, (I.A.D.S.) University of Lagos in a project titled “Yorùbá Indigenous Advertisement”
He is also a Translator, Newscaster and a Radio Presenter in UNILAG103.1FM.
He has received numerous academics awards. He is a Yorùbá Teacher, a Poet and an advocate of Yorùbá culture..
Àṣẹ̀sẹ̀tẹ̀jáde ìròyìn látọwọ́ọ Babátúndé Pópóọlá
Fún Ayẹyẹ Àìsùn Ọdún Tuntun àwọn Ilé-Ìwé ní Moscow, àwọn orin kan ò bójúmu
Ní àpapọ̀, àtòjọ náà ní àwọn olórin àti ẹgbẹ́ eléré 29. Díẹ̀ nínú wọn, bíi Little Big àti Manizha, ti ṣojú orílẹ̀-èdè Russia rí ní ìdíje Eurovision fún ọdún púpọ̀ látẹ̀yìnwá. Gbogbo wọn pata ni wọ́n bu ẹnu àtẹ́ lu ìkọlù orílẹ̀-èdè Russia sí Ukraine ní gbangba
Súyà Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà!
Mọ́là kan ni a rí níbí tí ó jókòó sídìí Àtẹ Súyà rẹ̀ Súyà (tí wọ́n ń pè é báyìí pé Sú-yá-à) Ìyẹn ni orúkọ ìjànjá-ẹran kan tí a ń yan lórí ayanran tó fẹjú, pẹ̀lú òróró, àlùbọ́sà àti iyọ̀. Súyà jẹ́ gbajúgbajà ohun jíjẹ láàárín àwọn ọlọ́rọ̀ àti bọ̀rọ̀kìní...
Boji rè é, Ajá tí ó máa ń jayé orí i rẹ̀ kiri ìgboro Istanbul nínú ọkọ̀ èrò
Ẹ pàdé Boji, Ajá kan ni Istanbul tí ó máa ń wọ ọkọ̀ èrò kiri ìgboro lójoojúmọ́.
Rising Voices’ Activismo Lenguas gba Àmì-ẹ̀yẹ Èdè Abínibí Àgbáyé
"Àmì-ẹ̀yẹ yìí dúró gẹ́gẹ́ bí ipa tí àwọn ajìjàngbara èdè lórí ẹ̀rọ-ayárabíàṣá ń ní jákèjádò agbègbè Latin Amẹ́ríkà àti arapa ribiribi iṣẹ́ wọn."
Ìlàkàkà láti fi òpin sí òkúrorò SARS ẹ̀ka ilé-isẹ́ ọlọ́pàá ilẹ̀ Nàìjííríà ń tẹ̀síwájú.
Ìbéèrè lórí ẹni tí ó ń darí àwọn Ọlọ́pàá àti ikọ̀ SARS kò tíì fi gbogbo ara rí ìdáhùn. Ìwé-òfin ilẹ̀ náà gbágbára ìdárí lé ààrẹ lọ́wọ́, ó sì gbé agbára àmójútó lé Ọ̀gá àgbà ilé iṣẹ́ Ọlọ́pàá lọ́wọ́.
‘Boca de Rua': Ìwé ìròyìn ilẹ̀ brazil láti ọwọ́ àwọn ènìyàn tí ó ń gbé ní ojú òpópónà
Wọ́n dá a sílẹ̀ ní nǹkan bi 20 ọdún sẹ́yìn. ‘Boca de Rua’ nìkan ni ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ Àwọn Ìwé Ìròyìn Ẹsẹ̀kùkú Àgbáyé tí àwọn ẹni tí ó ń sun ojú títì ń ṣe jáde.
Àwọn ìdílé l’órílẹ̀-èdè Kenya fi ara kááṣá látàrí ipa ìfọjọ́-kún ilé-ìwé tí ó wà ní títì pa
Látàrí títì pa àwọn ilé-ìwé ní orílẹ̀-èdè Kenya, àìdọgba ti kọjá bẹ́ẹ̀. Àwọn amòye nídìí ètò-ẹ̀kọ́ fẹ́ kí ìjọba tún iná ètò-ẹ̀kọ́ dá látì lè jẹ́ kí ìkẹ́kọ̀ọ́ ó kárí tẹrútọmọ