Babátúndé Pópóọlá

BABATÚNDÉ ỌLÁṢAYỌ̀ PÓPÓỌLÁ holds a Bachelor of Degree in view in Linguistics/Yoruba from University of Lagos. His final year thesis is on “The used of Oral Literature in Afọ̀njá movie” Supervisor: Caleb S. Ọ̀wọ́adé M.A. (LAGOS)

He is currently a Research Assistant to Prof. Ọlàdiípọ̀ Ajíbóyè of the Department of Linguistics African and Asian Studies, Unilag and Dr. Abísóyè Ẹlẹ́shin of Institute of African and Diaspora Studies, (I.A.D.S.) University of Lagos in a project titled “Yorùbá Indigenous Advertisement”

He is also a Translator, Newscaster and a Radio Presenter in UNILAG103.1FM.

He has received numerous academics awards. He is a Yorùbá Teacher, a Poet and an advocate of Yorùbá culture..

Ímeèlì Babátúndé Pópóọlá

Àṣẹ̀sẹ̀tẹ̀jáde ìròyìn látọwọ́ọ Babátúndé Pópóọlá

Fún Ayẹyẹ Àìsùn Ọdún Tuntun àwọn Ilé-Ìwé ní Moscow, àwọn orin kan ò bójúmu

Ìkùrìrì RuNet  31 Ọ̀pẹ 2022

Ní àpapọ̀, àtòjọ náà ní àwọn olórin àti ẹgbẹ́ eléré 29. Díẹ̀ nínú wọn, bíi Little Big àti Manizha, ti ṣojú orílẹ̀-èdè Russia rí ní ìdíje Eurovision fún ọdún púpọ̀ látẹ̀yìnwá. Gbogbo wọn pata ni wọ́n bu ẹnu àtẹ́ lu ìkọlù orílẹ̀-èdè Russia sí Ukraine ní gbangba

Súyà Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà!

Mọ́là kan ni a rí níbí tí ó jókòó sídìí Àtẹ Súyà rẹ̀ Súyà (tí wọ́n ń pè é báyìí pé Sú-yá-à) Ìyẹn ni orúkọ ìjànjá-ẹran kan tí a ń yan lórí ayanran tó fẹjú, pẹ̀lú òróró, àlùbọ́sà àti iyọ̀. Súyà jẹ́ gbajúgbajà ohun jíjẹ láàárín àwọn ọlọ́rọ̀ àti bọ̀rọ̀kìní...