BABATÚNDÉ ỌLÁṢAYỌ̀ PÓPÓỌLÁ holds a Bachelor of Degree in view in Linguistics/Yoruba from University of Lagos. His final year thesis is on “The used of Oral Literature in Afọ̀njá movie” Supervisor: Caleb S. Ọ̀wọ́adé M.A. (LAGOS)
He is currently a Research Assistant to Prof. Ọlàdiípọ̀ Ajíbóyè of the Department of Linguistics African and Asian Studies, Unilag and Dr. Abísóyè Ẹlẹ́shin of Institute of African and Diaspora Studies, (I.A.D.S.) University of Lagos in a project titled “Yorùbá Indigenous Advertisement”
He is also a Translator, Newscaster and a Radio Presenter in UNILAG103.1FM.
He has received numerous academics awards. He is a Yorùbá Teacher, a Poet and an advocate of Yorùbá culture..
Àṣẹ̀sẹ̀tẹ̀jáde ìròyìn látọwọ́ọ Babátúndé Pópóọlá láti Ọ̀wàrà , 2020
Ìlàkàkà láti fi òpin sí òkúrorò SARS ẹ̀ka ilé-isẹ́ ọlọ́pàá ilẹ̀ Nàìjííríà ń tẹ̀síwájú.
Ìbéèrè lórí ẹni tí ó ń darí àwọn Ọlọ́pàá àti ikọ̀ SARS kò tíì fi gbogbo ara rí ìdáhùn. Ìwé-òfin ilẹ̀ náà gbágbára ìdárí lé ààrẹ lọ́wọ́, ó sì gbé agbára àmójútó lé Ọ̀gá àgbà ilé iṣẹ́ Ọlọ́pàá lọ́wọ́.