BABATÚNDÉ ỌLÁṢAYỌ̀ PÓPÓỌLÁ holds a Bachelor of Degree in view in Linguistics/Yoruba from University of Lagos. His final year thesis is on “The used of Oral Literature in Afọ̀njá movie” Supervisor: Caleb S. Ọ̀wọ́adé M.A. (LAGOS)
He is currently a Research Assistant to Prof. Ọlàdiípọ̀ Ajíbóyè of the Department of Linguistics African and Asian Studies, Unilag and Dr. Abísóyè Ẹlẹ́shin of Institute of African and Diaspora Studies, (I.A.D.S.) University of Lagos in a project titled “Yorùbá Indigenous Advertisement”
He is also a Translator, Newscaster and a Radio Presenter in UNILAG103.1FM.
He has received numerous academics awards. He is a Yorùbá Teacher, a Poet and an advocate of Yorùbá culture..
Àṣẹ̀sẹ̀tẹ̀jáde ìròyìn látọwọ́ọ Babátúndé Pópóọlá láti Ògún , 2020
Àwọn ìdílé l’órílẹ̀-èdè Kenya fi ara kááṣá látàrí ipa ìfọjọ́-kún ilé-ìwé tí ó wà ní títì pa
Látàrí títì pa àwọn ilé-ìwé ní orílẹ̀-èdè Kenya, àìdọgba ti kọjá bẹ́ẹ̀. Àwọn amòye nídìí ètò-ẹ̀kọ́ fẹ́ kí ìjọba tún iná ètò-ẹ̀kọ́ dá látì lè jẹ́ kí ìkẹ́kọ̀ọ́ ó kárí tẹrútọmọ