Ìròyìn nípa A journey into African music
Ìdílé Kútì tí ń fẹ̀hónúhàn nípasẹ̀ orin àti àwọn ọmọ Nigeria mìíràn tí wọ́n kọrin táko ẹlẹ́yàmẹ̀yà
Àwọn ìdílé Kútì ti gbógun ti àwọn adarí burúkú nípasẹ̀ orin. Bákan náà, àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nigeria bí Sonny Okosun, Majek Fashek àti Onyeka Onwenu jà láti rí i pé wọ́n dá Nelson Mandela sílẹ̀ ní ọgbà ẹ̀wọ̀n.
Orin ẹ̀hónú: àwọn ọ̀dọ́mọdé òǹkọrin ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń kọrin tako ìwà ìrẹ́jẹ láwùjọ
Àwọn ọ̀dọ́mọdé olórin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti tẹ̀síwájú nínú àṣà kíkọ orin tako ìrẹ́jẹ láwùjọ. Èhónú #EndSARS ṣe ìtanijí ọkàn wọn sí ìkópa nínú ètò òṣèlú, eléyìí tí ó ti ń wòòkùn.