Ìròyìn nípa Nàìjíríà
Sísọnù sínú ògbufọ̀: Ìdí tí Atúmọ̀ Google ṣe ń kùnà — nínú títúmọ̀ èdè Yorùbá — àti àwọn èdè mìíràn
Bí àwọn iléeṣẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ ṣe ń gbìyànjú láti mú kí ògbufọ̀ èdè wà lárọ̀ọ́wọ́tó fún onírúurú èdè lórí ayélujára, ni àríyànjiyàn àti ìpèníjà ń gbérí — pàápàá jù lọ ti àṣe déédéé àti ìtumọ̀ ọ̀rọ̀ ọlọ́pọ̀ ìtumọ̀.
Ọ̀rọ̀ àyálò nínú èdè Yorùbá: Bí èdè ṣe yí padà
Lílo àwọn ojúlówó ọ̀rọ̀ èdè Yorùbá pọ́nbélé máa ń mú kí àṣà — ó gbòòrò — tí yóò sí máa gbilẹ̀.
Sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ ní Nàìjíríà darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́-ẹ wọn láti sààmì ayẹyẹ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé ọdún-un 2020
Àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀-ọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà darapọ̀ mọ́ àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ orí ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lágbàáyé láti sààmì Àyájọ́ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé lọ́jọ́ 13 oṣù Èrèlé ọdún-un 2020 àti láti fọn rere iṣẹ́ ìdàgbàsókè àgbà-ńlá ayé tí ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ń ṣe.
Twitter di pápá ìròyìn ayédèrú lásìkò Ìdìbò ọdún-un 2019 ní Nàìjíríà
Twitter di pápá ayédèrú ìròyìn ìtako ẹ̀yà kan àti ìsọkiri ṣáájú ìdìbò, lásìkò ìdìbò àti lẹ́yìn ìdìbò ti ọdún-un 2019 lórílẹ̀-èdèe Nàìjíríà
Kíni ìdí irẹ̀ tí Donald Trump ṣe l'ókìkí ní Nàìjíríà?
Ratings for US President Donald Trump’s handling of world affairs are largely negative around the world. But not in Nigeria.
Ẹ̀rọ Alátagbà ni a fi gbé àwọn ìròyìn irọ́ àti ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹyà jáde lásìkò ìdìbò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà
Ìbò ọdún-un 2019 orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà rí àwọn ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin láìròtẹ́lẹ̀ nípasẹ̀ẹ ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ àti ọ̀nà ìtànkálẹ̀ ìròyìn lórí ayélujára, pabambarì lóríi gbàgede Twitter.
Ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà yóò pa òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ lórí ayélujára ní Nàìjíríà
Ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà náà yóò pa òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ lórí ayélujára, sọ ìtakò ìjọba d'ẹ̀ṣẹ̀ àti sọ ìṣánpa ẹ̀rọ ayélujára ní Nàìjíríà dòfin.
#SexForGrades: Ètò Alálàyé-afẹ̀ríhàn tú àṣìírí ìwà ìyọlẹ́nu ìbálòpọ̀ ní àwọn Ifásitìi Ìwọ-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀
Professors who harass female students and pressure them for sex in return for grades or school admission has become the norm in many universities in Nigeria and Ghana.
Pẹ̀lú àìbalẹ̀-ọkàn tí ó ń pọ̀ sí i ní ìmúra ìbò ààrẹ ọdún-un 2019, Ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń bẹ̀rùu pípa ẹ̀rọ-ayélujára
Lílo ẹ̀rọ-alátagbà fún pípe àkíyèsí sí ìrúfin ìjọba àti ìwà tí kò bá òfin mu ti fa ìbẹ̀rù wípé ìtẹríbọlẹ̀ ní orí ayélujára ní àsìkò ìbò tí ó ń bọ̀.
Àwọn ọ̀gágun ajagun fẹ̀yìntì orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wọ̀yáàjà láti nípa lórí ètò ìdìbò ọdún-un 2019
Olusegun Obasanjo, former military head of state and later Nigeria’s democratically elected president, has consistently criticized successive governments in Nigeria.